December 2-8
SÁÀMÙ 113-118
Orin 127 àti Àdúrà | Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)
1. Kí La Máa San Pa Dà fún Jèhófà?
(10 min.)
Jèhófà ń dáàbò bò wá, ó ń fi inúure hàn sí wa, ó sì máa ń gbà wá (Sm 116:6-8; w01 1/1 11 ¶13)
A lè fi hàn pé a mọrírì ohun tí Jèhófà ń ṣe fún wa tá a bá ń pa àwọn àṣẹ rẹ̀ mọ́, tá a sì ń fi ìlànà ẹ̀ sílò nígbèésí ayé wa (Sm 116:12, 14; w09 7/15 29 ¶4-5)
A tún lè san oore Jèhófà tá a bá ń “rú ẹbọ ọpẹ́” sí i (Sm 116:17; w19.11 22-23 ¶9-11)
2. Àwọn Ẹ̀kọ́ Iyebíye Míì
(10 min.)
Sm 116:15—Àwọn wo làwọn “ẹni ìdúróṣinṣin” Ọlọ́run tí Bíbélì yìí ń sọ? (w12 5/15 22 ¶1-2)
Àwọn ẹ̀kọ́ iyebíye wo lo rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí tí wàá fẹ́ sọ?
3. Bíbélì Kíkà
(4 min.) Sm 116:1–117:2 (th ẹ̀kọ́ 2)
4. Má Bẹ̀rù Láti Sọ Òótọ́ Ọ̀rọ̀—Ohun Tí Jésù Ṣe
(7 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ káwọn ará wo FÍDÍÒ náà, kẹ́ ẹ sì jíròrò lmd ẹ̀kọ́ 12 kókó 1-2.
5. Má Bẹ̀rù Láti Sọ Òótọ́ Ọ̀rọ̀—Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Jésù
(8 min.) Ìjíròrò tó dá lórí lmd ẹ̀kọ́ 12 kókó 3-5 àti apá “Tún Wo.”
Orin 60
6. Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ
(15 min.)
7. Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ
(30 min.) bt orí 19 ¶1-5, àwọn àpótí ojú ìwé 149-150